Am so happy to have found this your channel have always want to know more about our history pls sir can u tell us about ogunmola bashorun ibadan I watch the movie but I think it’s not complete
Ilugun wà ní Abẹ́òkúta.. Orile-Ilugun tún wà ní ti a ba nlọ si Ìbàdàn (níbi tí ẹ ti ṣe eto yìí).. Àgọ́-Ìkà wá ní Abẹ́òkúta. Ìbàdàn-Gbágùrá na wa ni Abẹ́òkúta. Bẹ́ẹ̀ sì ni Ọ̀jọ́ọ̀-Gbágùrá àti Ìdó-Gbagura.. Àwọn àdúgbò yìí ni wón ńpè ni orílù.. Àti àwọn bíi Ake, Ìjẹmọ̀, Itokò, Kenta, Ìkọpa, Ikija, Iberekodo, Iláwọ, Idomapa etc. Bí àdúgbò ni wọ́n ṣe rí nínú ìlú Abẹ́òkúta. Gbogbo wọn ni wọ́n sì ní àwọn olóyè ìlú wọn bíi Olúwò, Balogun, etc. Ó sì ni ìpá tí wọ́n nko lábẹ́ Ọba wọn.. Fún àpẹrẹ ẹni tó bá jẹ Balogun Iláwọ ni ó máa ńjẹ oyè Seriki Òkè-Ọnà.. Wọ́n ni bí wọ́n ṣe to bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ títí dé Ẹ̀gbá Aláké àti òye Ẹ̀gbá.. Ayafi àwọn òye idalola nìkan tí wọ́n ké mú ọmọ ìlú tàbí ẹnikẹ́ni tó bá ṣe oun ribiribi sì ìlú. Fún àpẹẹrẹ bàbá wa J O. Ṣodimu (James) ni wọ́n jẹ́ Balogun Iláwọ ni igba aiyé wọn.. Àwọn ni bàbá fún eléré àti agbohunsafefe ẹ̀gbọ́n wa Yẹmi Ṣodimu.. Baba tiwa (tèmi) jẹ Lẹ́mọ Iláwọ, ní 1974 tàbí 1975.. Chief G Ó Kashimawo.. Òye ìlú ni ti wọ́n máa nlò fún ìpàdé dáadáa.. Teacher sì ni bàbá ni gbogbo ojo aiyé wọn.. Ẹ̀gbá ni mi
Oluko Agba..... You are the best in good story of Yoruba land. God will surely blessed you abundantly.
I'm enjoying this Ajeh 😊😘😉
I like olamilekan’s question about Ibadan and iba odan
Ẹ ṣe gan
May Almighty Allah bless you and your generation
Thank very much, Mr. Lekan, for requesting clarification about Lagelu’s era in Ibadan! I had been pondering about this matter, too.
Mo má ń gbádùn bí Ọlamilekan ṣe má ń béèrè ìbéèrè.. Ọ́ máa ń béèrè ìbéèrè dáadáa..
Am so happy to have found this your channel have always want to know more about our history pls sir can u tell us about ogunmola bashorun ibadan I watch the movie but I think it’s not complete
Ilugun wà ní Abẹ́òkúta.. Orile-Ilugun tún wà ní ti a ba nlọ si Ìbàdàn (níbi tí ẹ ti ṣe eto yìí).. Àgọ́-Ìkà wá ní Abẹ́òkúta. Ìbàdàn-Gbágùrá na wa ni Abẹ́òkúta. Bẹ́ẹ̀ sì ni Ọ̀jọ́ọ̀-Gbágùrá àti Ìdó-Gbagura.. Àwọn àdúgbò yìí ni wón ńpè ni orílù.. Àti àwọn bíi Ake, Ìjẹmọ̀, Itokò, Kenta, Ìkọpa, Ikija, Iberekodo, Iláwọ, Idomapa etc. Bí àdúgbò ni wọ́n ṣe rí nínú ìlú Abẹ́òkúta. Gbogbo wọn ni wọ́n sì ní àwọn olóyè ìlú wọn bíi Olúwò, Balogun, etc. Ó sì ni ìpá tí wọ́n nko lábẹ́ Ọba wọn.. Fún àpẹrẹ ẹni tó bá jẹ Balogun Iláwọ ni ó máa ńjẹ oyè Seriki Òkè-Ọnà.. Wọ́n ni bí wọ́n ṣe to bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ títí dé Ẹ̀gbá Aláké àti òye Ẹ̀gbá.. Ayafi àwọn òye idalola nìkan tí wọ́n ké mú ọmọ ìlú tàbí ẹnikẹ́ni tó bá ṣe oun ribiribi sì ìlú. Fún àpẹẹrẹ bàbá wa J O. Ṣodimu (James) ni wọ́n jẹ́ Balogun Iláwọ ni igba aiyé wọn.. Àwọn ni bàbá fún eléré àti agbohunsafefe ẹ̀gbọ́n wa Yẹmi Ṣodimu.. Baba tiwa (tèmi) jẹ Lẹ́mọ Iláwọ, ní 1974 tàbí 1975.. Chief G Ó Kashimawo.. Òye ìlú ni ti wọ́n máa nlò fún ìpàdé dáadáa.. Teacher sì ni bàbá ni gbogbo ojo aiyé wọn.. Ẹ̀gbá ni mi
Thanks for this
May Almighty Allah increase your knowledge
Orisi kokoro kan wa, ti o n je "ogongo" to n gbe inu ope ( palm tree)
Pls sir tell us story of ikire apomu.